Charleans Publication     
…… upholding the legacy

Current News Update In Yoruba - BBC Worldwide Service











News From The BBC

A Yoruba Perspective


Perimenopause: Wo àwọn ọ̀nà mẹ́fà láti mójútó ìlera lásìkò tí nǹkan oṣù obìnrin ti fẹ́ dúró
Perimenopause jẹ́ àsìkò tó máa ń wáyé ṣáájú kí obìnrin má tò rí nǹkan oṣù mọ́, nígbà tí àwọn ẹ̀yà ara obìnrin bá ń yípadà, táwọn ẹ̀yà ara tó wà fún ọmọ bíbí bá ń lọ sílẹ̀.

Ayẹyẹ ìfilọ́lẹ̀ Póòpù Leo XIV wáyé, Tinubu, Zelensky àtọ̀pọ̀ olórí orílẹ́èdè àgbáyé péjú
Aarẹ orilẹede Ukraine, Volodymyr Zelensky ati Igbakeji Aarẹ Amẹrika, JD Vance wa lara awọn olujọsin ni St. Peter's Square nibi ifilọlẹ Poopu Leo XIV.

Ìjàmbá ọkọ̀ gbẹ̀mí èèyàn méje, àwọn mẹ́rìndínlógún míì farapa
Adarí àjọ tó ń rí sí ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ní ìpínlẹ̀ Niger ìyẹn Niger State Emergency Management Agency, NSEMA, Abdullahi Baba-Arah ló kéde ìròyìn náà nínú àtẹ̀jáde kan tó fi léde Àìkú.

Kí ló ṣẹlẹ̀ sí àgbà òṣèré Yemi My Lover tó fi ké gbàjarè pé òun nílò ìrànlọ́wọ́?
Yemi My lover, tó di ìlú mọ̀ọ́ká fún eré rẹ̀, Yemi My Lover tó gbé jáde lọ́dún 1993 ṣàlàyé àwọn ìlàkàkà tó ń kò lójú láti ìgbà náà.

Ajínigbé ṣekúpa alága ẹgbẹ́ APC l'Ondo lẹ́yìn tí wọ́n kọ́kọ́ gba ₦5m owó ìtúsílẹ̀
Nigba to n fidi iroyin naa mulẹ, alaga ijọba ibilẹ Ose, Kolapo Ojo sọ pe eto abo agbegbe Ifon ati ijọba ibilẹ Ose ti buru kọja afẹnusọ.

Kọngílá parí títì, àgbàrá òjò wọ́ọ lọ lọ́jọ́ kejì, Gómìnà Adeleke bá fárígá l'Osun
Adugbo Aduramigba, to wa ni Ido-Osun, ni ijọba ibile Egbedore ni iṣẹlẹ naa ti waye.

Fukushima: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ilẹ̀ ríru Japan tó mú ẹ̀mí 16,000 èèyàn lọ
Gege bi awọn onkọtan ṣe sọ, yatọ si isẹlẹ Chernobyl to waye lọdun 1986 ni Ukraine, ko tun si eyii to buru to iṣẹlẹ naa lagbaye.

Èèyàn 27 tún kú nínú ìjamba ọkọ̀ ojú omi ní Kwara
Ọkan lara awọn ti ori koyọ ninu ijamba ọkọ oju omi naa sọ pe ọwọ afẹfẹ iji lile kan to nbọ wa si ọgangan ọkọ naa lo da a nu si agbami.

Ìdí tí mo fi pè fún àtúntò ìgbìmọ̀ àwọn ọba l' Oyo -Seyi Makinde
Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo ti bẹrẹ igbesẹ lati mu atunṣe ba ofin igbimọ lọbalọba ati ijoye nipinlẹ Oyo.

Ohun tí a mọ̀ nípa afurasí tọ́wọ́ aráàlù tẹ̀ fẹ́sùn pé ó fẹ́ jí ọmọ gbé ní Ilorin
Nínú fídíò kan tó gba orí ayélujára ni àwọn èèyàn kan ti ń bèèrè lọ́wọ́ afurasí náà tó pe ara rẹ̀ ní Pedro pé kí ló wá ṣe ní agbègbè náà tó sì ń fún wọn lésì pé òun fẹ́ jí ọmọ gbé ni.

Báyìí ni Boko Haram ṣe ń lo Tiktok fún ìpolongo ní Naijiria
Awọn agbebọn tun ṣafihan awọn ibọn lori opo ayelujara Tiktok pẹlu awọn ohun ija oloro miiran ati owo ninu oṣu kẹrin.

Àbọ̀ ìwádìí BBC rèé lórí ìrẹsì tí wọ́n ní ó ń pààyàn láti Seme
BBC kan si Abiodun Fareed Ayodele ti ọpọ eeyan mọ si Faredo ni Benin lori ọrọ yii, o ni iroyin ẹlẹjẹ lasan ni.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Kí ló kàn fún Simon Ekpa lẹ́yìn tí ìjọba Finland fẹ̀sùn ìdìtẹ̀mọ́jọba kàn án?
Awọn ẹsun miiran ti wọn tun fi kan ni iwa ọdaran ati kikuna lati san owo ori, to si n lo ọna eburu lati ma san owo ori naa..

Ṣó o l'áyà! Ẹ wo bí Eniola Ajao ṣe fakọyọ lórí ètò tí BBC fi n dàn ìmọ̀ èdè Yorùbá wò
Gbajumọ oṣere, Eniola Ajao kopa lori eto Ṣo o laya, lati fi imọ rẹ han nipa ede Yoruba

Ọlọ́pàá ń lo àyẹ̀wò DNA láti ṣàwárí ìyá àwọn ọmo tí wọ́n rí nínú àpò lẹ́bá ọ̀nà
Ninu oṣu Kinni ọdun 2025 yii ni ajọ kan ti kii ṣe ti ijọba kede pe oun yoo san £20,000 fun ẹnikẹni to ba le ṣamọna bi ijọba yoo ṣe ri iya tabi awọn obi ọmọ naa.

Njẹ́ o ti gbọ́ nípa àwọn ìlú mẹ́fà yìí níbi tí òòrùn ò kìí wọ̀ rárá?
Akojọpọ mẹfa lara awọn ibi ti oorun o ki ti n wọ nilẹ aye

Ọdún ìtẹ́ ọba nìkan ni mo ti gbọdọ̀ jó lẹ́ẹ̀kan lọ́dún - Olomu ti Omu-Aran
Afin Olomu ilu Omu-Aran, Ọba Abdulraheem Oladele Adeoti, nibi ti ọdun naa ti waye ko gba ẹsẹ.

Òkò ọ̀rọ̀ ń bọ́ bí Ibadan àti Oyo ṣe ń tahùn síra wọn lórí ẹni tí ipò alága ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba l'Oyo tọ́ sí
Lásìkò tí wọn ń bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀, Bode Durojaye tíí ṣe Agbẹnusọ fún Aláàfin Oyo àti Nurudeen Akinade, Baálẹ̀ fún àwọn Mọ̀gàjí ilẹ̀ Ibadan sọ òkò ọ̀rọ̀ lu ara wọn pẹ̀lú ìtàn ńlá.

"Ẹ gbà wá, ọdún kẹ̀ta rèé tí a ti ní iná ọba gbẹ̀yìn ní Ariwa Yewa, tírélà Dangote ló ba òpó iná wa jẹ́"
Jagunmolu Igbogila, Abdul Jelil Anisere, sọ pe o to ilu bi ogun labẹ ijọba Ariwa Yewa ti ko ni ina ọba bayii.

'Ojúbọ̀rọ̀ kọ́ ni mo fi débí, àtẹ̀jíṣẹ́ ikú ni mó ń gbà'- Ẹ̀yà Afrikaner tó di àtìpó l'America
Kleinhaus ati ọpọ eeyan mi-in ti wọn jẹ alawọ funfun lati South Africa di ero ilẹ America, labẹ iṣakoso Aarẹ Donald Trump. Aarẹ sọ pe oun fẹẹ da aabo bo wọn kuro nibi iyasọtọ, idẹyẹsi ti wọn n koju, bo tilẹ jẹ pe South Africa ti sọ pe ko sohun to jọ bẹẹ lọdọ awọn.

"Ọgbẹ́ ọkàn ló jẹ́ pé Faith, ọmọ mi pa ara rẹ̀ tórí ó gba máàkì kékeré nínú èsì ìdánwò JAMB"
Opesusi Oluwafemi, tíí ṣe bàbá Faith, ọmọbìnrin tó pa ara rẹ̀ torí máàkì kékeré tó gbà nínú èsì ìdánwò JAMB, bá BBC sọ̀rọ̀ nípa bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé, irú èèyàn tí ọmọ rẹ̀ jẹ́ àti ipò ìbànújẹ́ tó ẹbí rẹ̀ wà.

Àtúnṣe ìdánwò JAMB dàpọ̀ mọ́ ti WAEC, àwọn òbí figbe ta lórí ìpòrúru ọ̀kàn fáwọn mọ wọn
Awọn obi awọn akẹ́kọọ to fẹ tun idanwo JAMB se n pe fun isunsiwaju atunṣe idanwo naa .

Kí ló mú kí ìjọba Kwara gbé ilé ẹ̀kọ́ girama méjì tipa n'Ilorin?
Kọmisona feto ẹkọ ni ipinlẹ Kwara, Ọgbẹni Ọlọhungbẹbẹ Lawal, ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita pe ijọba ti awọn ile ẹkọ naa latari aawọ to bẹ silẹ laarin awọn akẹkọọ lati ile ẹkọ mejeeji.

Ọdún Egúngún àgbáyé sọkutu wọ̀wọ̀ nílùú Ibadan, àlàyé rèé lórí ìsesí egúngún pàtàkì mẹ́wàá tó pitú
Jakejado orilẹede Naijiria ati ilẹ okere ni ọpọ aṣoju awọn idile ti wọn ti n gbe awọn Egungun ti peju pesẹ, fun ajọyọ t'ọdun yii.

"Ìyàwó àti ọmọ mi márùn-ún kú lọ́jọ́ kan ṣoṣo lẹ́yìn tí wọ́n jẹ ìrẹsì tán"
Ọkunrin naa, Arinze Robinson Ahalu, ṣalaye ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu BBC pe irẹsi lawọn ọmọ oun ati iyawo jẹ lọjọ naa, ti wọn si gba ibẹ ku.

Jumoke George tí mọ ibi tí ọmọ rẹ̀ àmọ́ nǹkan kò fara rọ fún-un níbẹ̀ - Biola Bayo
Nínú fọ́nrán ohùn àti àwòrán kan tó gba orí ayélujára, ni gbajúmọ̀ òṣèré tíátà, Jumoke George pẹlu omije loju ṣalaye pe, ọdun kẹrin ree ti ọmọ rẹ obinrin ti di awati, to si tun da ọmọ meji silẹ fun oun lati maa tọju wọn.

Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn òbí fẹ́ kí àjọ JAMB fagilé gbogbo èsì ìdánwò UTME tó jáde torí àṣìṣe tó wà níbẹ̀
Awọn eeyan yii tako igbesẹ ajọ JAMB lati tun idanwo naa ṣe nipinlẹ Eko ati lawọn ipinlẹ ẹkun ila oorun guusu Naijiria nikan.

Ìyàwó ilé tó di ògbóǹtarìgì nínú ìdíje àgbáyé fáwọn èèyàn tó sán eegun
Igbe aye Roya n sọ nipa obinrin ti aṣa da lọwọ kọ amọ ti o ti dominira, to si jẹ awokọṣe fawọn obinrin ẹgbẹ rẹ.

Lẹ́yìn iṣẹ́ abẹ kejì ní ikùn rẹ̀, Taiwo Awoniyi jí sáyé padà, ó kúrò ní ẹsẹ̀ kan ayé, ẹsẹ̀ kan ọ̀run
Awoniyi ni wọn gbe digbadigba lọ ile iwosan ni ọjọ Aje, lẹyin to kọlu opo oju ile bọọlu lori paapa nigba ti ikọ agbabọọlu rẹ n koju ikọ Leicester City lọjọ Aiku to kọja.

"Ojú ọ̀nà Ikare sí Ogbagi di pàkúté ikú, ẹ̀mí arìnrìnàjò ń bọ́ púpọ̀ torí ìjàmbá ọkọ̀, ìkọlù adigunjalè àtàwọn ajínigbé"
BBC Yorùbá ṣe àbẹ̀wò sí ojú ọ̀nà Ikare si Ogbagi níbi tí ìjàmbá ọkọ̀, adigunjalè àtàwọn ajínigbé ti ń gba ẹ̀mí ọ̀pọ̀ arìnrìnàjò láìníye.

Kí ló ń fa ìwà ìṣekúpa ẹnìkejì ẹni tó ń wáyé lójúmọ̀ ní Naijiria?
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Kano, SP Abdullahi Haruna Kiyawa ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Faraw ni ijọba Tarauni nipinlẹ Kano.

Wo eré tíátà mẹ́wàá tó sọ fíìmù Yorùbá di ìlúmọ̀ọ́ká ní àgbáyé
BBC Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ àwọn eré tíátà mẹ́wàá ní èdè Yorùbá tí wọn gbé jáde lọ́pọ̀ ọdún sẹ́yìn, èyí tó ṣe àfihàn àṣà àti ìṣe wa fún gbogbo àgbáyé.

"Àwọn ológun wà níbí lóòótọ́, ṣùgbọ́n kò sí ààbò fún wa"
Ero awọn eeyan tẹlẹ ni pe ologun Naijiria pẹlu ajọṣepọ awọn orilẹede alamuleti, ti ṣẹgun Boko Haram, ṣugbọn ni bayii, ikọlu naa n waye leralera lati nnkan bii ọdun mẹta sẹyin.

Wo bí ìmọ̀ ẹ̀rọ àtọwọ́dá àti àsọdùn ṣe ń gbóríyìn fún olórí ológun
O le lọgọrun-un fidio bayii ti wọn lo imọ ẹrọ ti a mọ si AI ṣe, eyi to n ṣafihan Traoré bii akọni ọmọ ilẹ Afrika, ọpọ rẹ lo jẹ pe oun ti ko ri bẹẹ ni wọn n sọ. Ọpọlọpọ fidio bayii lo ti kun ori ayelujara kaakiri ẹkun Sahara ilẹ Africa lati ipari oṣu Kẹrin.

Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ‘ìrẹsì olóró’ tí wọ́n ló wọ ìpínlẹ̀ Ogun àti Eko
Gẹgẹ bi awọn to n pin ikilọ naa ka ṣe wi ninu awọn fọnran ohun wọn, oniṣowo kan ni wọn lo fi Ògún ṣepe nitori irẹsi rẹ ti wọn ji ko wọ Naijiria.

Ìdí tí Tinubu ṣe fi òfin de kíkó àwọn ọjà kan wọlé sí Nàíjíríà láti ilẹ̀ òkèèrè
Aarẹ Tinubu tun sọ gbedeke iye awọn akọṣẹmọṣẹ ilẹ okeere to le wọ Naijiria lati wa ṣiṣẹ tawọn ọmọ Naijiria naa le ṣe funra wọn.




Event Info

Click Here To See Info

1

Date: 2017-03-11

2

Openning Time: 6pm

3

Venue: Banquet Hall, Premier Hotel, Ibadan




Special Guest List

Click Here To See List

1

Distinquished Guest Of Honour: Bashorun Rotimi Obeisun

2

Special Guest Of Honour: Alhaji Olalekan Alli

3

Guest Of Honour: Bimbo Kolade

4

Father Of The Day: Prof B.B Adeleke

5

Chairman Of The Day: Majek Okunola OWOO









Share This Info

Click To See Info To Share

Enter the email address to send a link of this page to and submit

Social Networks

Share this info with your favourite social network



Copy And Paste

Copy the Link and paste anywhere on the web to promote